Postagens

Mostrando postagens de junho, 2022

Oni ni ajọdún ti Ọọni Ilé-Ifẹ̀ náá ikede ìlú Bahia gẹgẹbi Olú-ìlú Yorùbá ti gbogbo àwọn Amẹ́rikà

Imagem
  Lára abẹwo si orílẹ̀-èdè Brasíìlì ni o ṣù keje, ọdún 2018, Ọọni ile-Ifẹ náà, Ọba Adeyẹye Ogunwusi Ọjaja keji ni: “... àwọn ọmọ Yorùbá to wa kaakiri igun mẹrẹrin agbaye ko gbọdọ sọ ami idanimọ wọn nu, nitori ọmọ iya kan naa ni gbogbo awọn ọmọ Oodua bii Itsekiri, Edo, Ga, Anago, Igala, Lucumi, Tapa, ati Yoruba ti orisun wọn si wa ni ilu Ile Ifẹ...” Àwọn iran ti àwọn Ànàgó ni ode oni ìlú Brasílì kò le lo èdè náà fún àwọn ohun iṣe ti ojojumọ wọn. Sibẹsibẹ, àwọn orin, ijó, ìtan aye atijọ́, ounjẹ ati ẹ̀sin ń ṣiṣe ni ọpọ àgbègbé kaakiri orílẹ̀-èdè náà.   “... àwọn ọmọ Yorùbá to wa kaakiri igun mẹrẹrin agbaye ko gbọdọ sọ ami idanimọ wọn nu, nitori ọmọ iya kan naa ni gbogbo awọn ọmọ Oodua bii Itsekiri, Edo, Ga, Anago, Igala, Lucumi, Tapa, ati Yoruba ti orisun wọn si wa ni ilu Ile Ifẹ...” Àwọn iran ti àwọn Ànàgó ni ode oni ìlú Brasílì kò le lo èdè náà fún àwọn ohun iṣe ti ojojumọ wọn. Sibẹsibẹ, àwọn orin, ijó, ìtan aye atijọ́, ounjẹ ati ẹ̀sin ń ṣiṣe ni ọpọ àgbègbé kaak...