Loni ni Ọjọ́ a nṣe àjọ̀dún Òrìṣà Ọbalúwaye
Ẹ kúu déédéé àsikò yìí, ọmọ Oduduwa àtàtà kakiri agbaye Orúkọ tèmi ni Oluk ọ̀ Agba Adelson de Brito ti ọpọ eeyan m ọ̀ sí Mawo Adelson. Olori ẹsin ibilẹ̀ Òrìsà àti Vodun ti Afirika ni mi Olukọ Èdè àti àṣà Yorùba-Ànàgó ni mi. Ọmọ ọmọ ènìyàn Ànàgó ti wọ́n bi àti dagba ni Ilẹ̀ okeere ni mi. Àwọn obi mi bi mi ni Ìlú Salvador, Olu-ilu ipinlẹ̀ Baííà, ni orílẹ̀-èdè Burasili. Mo s ọ pẹ̀lú gbogbo yín lati ìlú yìí ni bayìí. Inu mi dun gan Ope lowo Eledumare Gbogbo irunmale ti ile Oduduwa fún mi anfaani yii, lati kopa ni eto yii, po pelo Ojogbon Mateus Aleluya Ṣe o mọ wipe ni Ìlú mi àwọn aláwọ̀ dúdú pọ̀ júlọ agbaye lẹhin Afirika? O ṣ ee ṣ e ti o mo wípè eya Ánàgó jẹ́ àw ọ n ọm ọ Oduduwa ti a ji lati agbegbe ti iwoorun il ẹ̀ aláwo dúdú, nipasẹ àwọn oniṣowo ẹrú lakoko iṣowo ẹrú? Se o mo wípè Gbogbo ijọsin Ọlọ́run ni imisi Eleduwa ni o si ni ere fún ẹ̀kọ́, fún ajọṣe, fún ikọ́ni ti o wa ninu òdodo? Bẹẹni, ẹyin ọmọ, kò si Igbagbọ akọkọ ati alailẹgbẹ ati iyas...